Nítorí ó wà ní àkọsílẹ̀ pé,“Ta ni ó mọ inú Oluwa?Ta ni yóo kọ́ Oluwa lẹ́kọ̀ọ́?”Ṣugbọn irú ẹ̀mí tí Kristi ní ni àwa náà ní.