Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Samuẹli Kinni 10:1 BIBELI MIMỌ (BM)

Nígbà náà ni Samuẹli mú ìgò òróró olifi kan, ó tú u lé Saulu lórí. Ó fi ẹnu kò ó lẹ́nu, ó sì wí fún un pé, “OLUWA fi àmì òróró yàn ọ́ ní olórí àwọn eniyan Israẹli. Ohun tí yóo sì jẹ́ àmì tí o óo fi mọ̀ pé OLUWA ló yàn ọ́ láti jọba lórí àwọn eniyan rẹ̀ nìyí:

Ka pipe ipin Samuẹli Kinni 10

Wo Samuẹli Kinni 10:1 ni o tọ