Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Nọmba 27:3-6 BIBELI MIMỌ (BM)

3. “Baba wa kú sinu aṣálẹ̀ láìní ọmọkunrin kankan. Kò sí lára àwọn ẹgbẹ́ Kora tí ó ṣọ̀tẹ̀ sí OLÚWA, ṣugbọn ó kú nítorí ẹ̀ṣẹ̀ tirẹ̀ ni.

4. Kí ló dé tí orúkọ baba wa yóo fi parẹ́ kúrò ninu ìdílé rẹ̀ nítorí pé kò ní ọmọkunrin? Nítorí náà, ẹ fún wa ní ilẹ̀ ìní láàrin àwọn eniyan baba wa.”

5. Mose bá bá OLUWA sọ̀rọ̀ nípa wọn,

6. OLUWA sì sọ fún un pé,

Ka pipe ipin Nọmba 27