Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Kronika Kinni 20:1 BIBELI MIMỌ (BM)

Nígbà tí àkókò òtútù kọjá, ní àkókò tí àwọn ọba máa ń lọ jagun, Joabu gbógun ti ilẹ̀ Amoni; wọ́n dó ti ìlú Raba. Ṣugbọn Dafidi dúró ní Jerusalẹmu. Joabu gbógun ti Raba, ó sì ṣẹgun rẹ̀.

Ka pipe ipin Kronika Kinni 20

Wo Kronika Kinni 20:1 ni o tọ