Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Jẹnẹsisi 24:23-26 BIBELI MIMỌ (BM)

23. Lẹ́yìn náà, ó bi í pé, “Jọ̀wọ́, kí ni orúkọ baba rẹ? Ǹjẹ́ ààyè ṣì wà ní ilé yín tí a lè wọ̀ sí ní alẹ́ yìí?”

24. Ó dá a lóhùn, ó ní, “Betueli, ọmọ tí Milika bí fún Nahori ni baba mi.”

25. Ó tún fi kún un pé, “A ní ọpọlọpọ koríko ati oúnjẹ ẹran, ààyè sì wà láti sùn ní ilé wa.”

26. Ọkunrin náà bá tẹríba, ó sì sin OLUWA,

Ka pipe ipin Jẹnẹsisi 24