Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Jẹnẹsisi 24:1-3 BIBELI MIMỌ (BM)

1. Abrahamu ti darúgbó, Ọlọrun sì ti bukun un ní gbogbo ọ̀nà.

2. Abrahamu sọ fún iranṣẹ rẹ̀ tí ó dàgbà jù ninu ilé rẹ̀, ẹni tí í ṣe alákòóso ohun gbogbo tí ó ní, pé, “Ti ọwọ́ rẹ bọ abẹ́ itan mi,

3. n óo sì mú kí o búra ní orúkọ OLUWA Ọlọrun ọ̀run ati ayé, pé o kò ní fẹ́ aya fún ọmọ mi lára àwọn ọmọbinrin ará Kenaani tí mò ń gbé,

Ka pipe ipin Jẹnẹsisi 24