Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Àwọn Adájọ́ 18:18 BIBELI MIMỌ (BM)

Nígbà tí àwọn marun-un náà lọ sí ilé Mika tí wọ́n sì kó àwọn ère rẹ̀ ati àwọn nǹkan oriṣa rẹ̀, alufaa náà bi wọ́n léèrè pé, “Irú kí ni ẹ̀ ń ṣe yìí?”

Ka pipe ipin Àwọn Adájọ́ 18

Wo Àwọn Adájọ́ 18:18 ni o tọ