Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Mátíù 22:20-22 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

20. ó sì bi wọ́n pé, “Àwòrán tabi èyí? Àkọlé tà sì ní?”

21. Wọ́n sì dáhùn pé, “Ti Késárì ni.”“Nígbà náà ni ó wí fún wọn pé,” “Ẹ fi èyí tí í ṣe ti Késárì fún Késárì, ẹ sì fi èyí ti ṣe ti Ọlọ́run fún Ọlọ́run.”

22. Nígbà tí wọ́n gbọ́ èyí, ẹnú yà wọ́n. Wọ́n fi í sílẹ̀, wọ́n sì bá tiwọn lọ.

Ka pipe ipin Mátíù 22