13. “Bí àwọn ènìyàn mi yóò bá gbọ́ tèmibí Ísírẹ́lì yóò bá tẹ̀lé ọ̀nà mi,
14. Ní kánkán ni èmi yóò ṣẹ́gun àwọn ọ̀tá wọnkí ń sì yí ọwọ́ mi padà sí ọ̀tá wọn!
15. Àwọn tí ó kórìíra Olúwa yóò tẹríba níwájú Rẹ̀.Ìjìyà wọn yóò sì pẹ́ títí láé
16. Ṣùgbọ́n a ó fi ọkà tí ó dára bọ́ ọ́ yínèmi ó tẹ́ ẹ yín lọ́rùn pẹ̀lú oyin inú àpáta.”