Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Sáàmù 58:3-7 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

3. Ní inú ìyá wọn wá, ni eniyàn búburú tí sìnà lojukan náà tí a ti bí wọnwọn a máa ṣèké.

4. Ọ̀rọ̀ wọn dà bí ọ̀rọ̀ ejò,gẹ́gẹ́ bí ti sèbé tí ó dítí Rẹ̀,wọn dàbí adití ejò paramọ́lẹ̀ tí ó di ara Rẹ̀ ni etí

5. Tí kò ní gbọ́ ìpè àwọn atinilójú,bí ó ti wù kí ó máa fi ọgbọ́n ṣe ìtujú tó.

6. Ká eyín ẹnu wọn, Ọlọ́run;ní ẹnu wọnká ọ̀gan àwọn ọmọ kìnnìún, Olúwa.

7. Jẹ́ kí wọn parẹ́ bí omi tó ń ṣàn lọ;nígbà tí ó bá fa ọfà Rẹ̀, kí ọ̀kọ̀ wọn kí ó ṣẹ́.

Ka pipe ipin Sáàmù 58