Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Sáàmù 36:9-12 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

9. Nítorí pé pẹ̀lú ù Rẹ ni orísun ìyè wà:nínú ìmọ́lẹ̀ Rẹ ni àwa yóò rí ìmọ́lẹ̀.

10. Mú ìṣeun ìfẹ́ ẹ Rẹ sí àwọn tí ó mọ̀ ọ́àti ìgbàlà Rẹ sí àwọn tí ó ní ìdúró ṣinṣin ọkàn!

11. Má ṣe jẹ́ kí ẹ̀ṣẹ̀ agbéragakí ó wá sí orí mi,kí ọwọ́ àwọn ènìyànbúburú sí mi ni ipò.

12. Níbẹ̀ ni àwọn oníṣẹ́ ẹ̀ṣẹ̀gbé subú sí:a Rẹ̀ wọ́n sílẹ̀,wọn kì yóò le è dìde!

Ka pipe ipin Sáàmù 36