Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Sáàmù 28:4-7 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

4. Ṣan ẹ̀ṣan wọn gẹ́gẹ́ bí isẹ́ wọnàti fún iṣẹ́ ibi wọn;gba ẹ̀san wọn gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ ọwọ́ wọn;kí o sì san ẹ̀ṣan wọn bí ó ti tọ́.

5. Nítorí pé wọn kò ka iṣẹ́ Olúwa sí,tàbí àwọn isẹ́ ọwọ́ Rẹ̀òun ó rún wọn wọlẹ̀kò sì ní tún wọn kọ́ mọ́.

6. Alábùkún fún ni Olúwa!Nítorí pé ó ti gbọ́ ohùn ẹ̀bẹ̀ mi.

7. Olúwa ni agbára mi àti aṣà mi;nínú Rẹ̀ ni mo gbẹ́kẹ̀lé; àní, ó sì ràn mí lọ́wọ́.ọkàn mi sì gbé sókè fún ayọ̀àni pẹ̀lú orin mi mo fi ọpẹ́ fún un.

Ka pipe ipin Sáàmù 28