Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Sáàmù 2:1-6 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

1. Èéṣe tí àwọn orílẹ̀ èdè fi ń dìtẹ̀,àti tí àwọn ènìyàn ń ṣe rìkísí asán?

2. Àwọn ọba ayé péjọ pọ̀àti àwọn ìjòyè gbìmọ̀ pọ̀sí Olúwaàti sí Ẹni àmì òróró Rẹ̀.

3. Wọ́n sọ pé, “Ẹ jẹ́ kí a fa ẹ̀wọ̀n wọn já,”“kí a sì ju ṣẹ́kẹ́ṣẹkẹ̀ wọn nù.”

4. Ẹni tí ó gúnwà lórí ìtẹ́ lọ́run rẹ́rìn-ín; Olúwa fi wọ́n rẹ́rìn-ín ẹlẹ́yà.

5. Nígbà náà ni ó bá wọn wí ní ìbínú Rẹ̀ó sì dẹ́rùba bà wọ́n ní ìrunú Rẹ̀, ó wí pé,

6. “Èmi ti fi ọba mi sí ipòlórí Síónì, òkè mímọ́ mi.”

Ka pipe ipin Sáàmù 2