Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Sáàmù 107:34-41 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

34. Ilẹ̀ eleso di aṣálẹ̀ nítorí ìwà búburú àwọn tí ó wà nínú Rẹ̀;

35. O sọ ihà di adágún omi àtiilẹ̀ gbígbẹ di oríṣun omi

36. Níbẹ̀ ó mú ẹni tí ebi ń pa wà,wọ́n sì pìlẹ̀ ibi tí wọn ó máa gbé

37. Wọn fún irúgbìn, wọ́n sì gbin ọgbà àjàràtí yóò ma so èso tí ó dára;

38. Ó bùkún wọn, wọ́n sì pọ̀ sí i ní iyekò sí jẹ́ kí ẹran ọ̀sìn wọn kí ó dín kù.

39. Nígbà náà, ọjọ́ wọn kúrú,ìnira, ìpọ́njú àti ìṣòro wọn sì dínkù

40. Ẹni tí ó da ẹ̀gàn lu ọmọ aládéó sì mú wọn rìn níbi tí ọ̀nà kò sí

41. Ṣùgbọ́n ó gbé aláìní sókè kúrò nínú ìniraó mú ìdílé wọn pọ̀ bi agbo ẹran

Ka pipe ipin Sáàmù 107