18. Ọwọ́ iná yọ ní ẹgbẹ́ àwọn ọmọ ẹ̀yin Rẹ̀;iná jo àwọn ènìyàn búburú.
19. Ní Hórébù wọ́n ṣe ẹ̀gbọ̀rọ̀ màlúùwọn sì sin òrìṣà tí a ṣe láti ara ìrìn.
20. Wọn pa ògo wọn dàsí àwòrán màlúù, tí ń jẹ koríko.
21. Wọ́n gbàgbé Ọlọ́run, ẹni tí í gbàwọ́nẹni tí ó ti ṣe ohun ńlá fún Éjíbítì,
22. Iṣẹ́ ìyanu ní ilẹ̀ Ámùàti ohun ẹ̀rù ni ẹ̀bá òkun pupa
23. Bẹ́ẹ̀ ní, ó sọ wí pé oun yóò pa wọ́n runbí kò ba ṣe tí Mósè, tí ó yàn,tí ó dúró níwájú ẹ̀yà náàtí ó pa ìbínú Rẹ̀ mọ́ láti má pa wọ́n run mọ́