Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Sáàmù 10:12-17 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

12. Dìde, Olúwa! Gbé ọwọ́ Rẹ̀ sókè, Ọlọ́run.Má ṣe gbàgbé àwọn olùpọ́njú.

13. Èeṣe tí ènìyàn búburú ṣe ń kẹ́gàn Ọlọ́run?Èéṣe tí o fi wí nínú ọkàn ara Rẹ̀,“Kò ní pé mí láti ṣe ìṣirò”?

14. Ṣùgbọ́n ìwọ, Ọlọ́run, ni o ri wàhálà àti ìrora;Ìwọ rò láti fi sí ọwọ́ Rẹ.talákà fara Rẹ̀ jin fún ọ;Ìwọ ni olùrànlọ́wọ́ àwọn aláìní baba.

15. Ṣẹ́ apá àwọn ènìyàn búburú àti ènìyàn ibi;pèé láti wa sírò fún iwà ìkà Rẹ̀tí a kò le è rí.

16. Olúwa ń jọba láé àti láéláé;àwọn orílẹ̀ èdè yóò ti ilẹ̀ Rẹ̀ ṣègbé.

17. Ìwọ́ gbọ, Olúwa, ìfẹ́ àwọn tí a ni lára;Ìwọ gbà wọ́n níyànjú, ó sì gbọ́ ìgbe wọn,

Ka pipe ipin Sáàmù 10