Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Onídájọ́ 7:21 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Nígbà tí ọkùnrin kọ̀ọ̀kan dúró ní ipò rẹ̀ yí ibùdó àwọn Mídíánì ká, gbogbo àwọn ọmọ ogun Mídíánì ń sá káàkiri, wọ́n ń pariwo bí wọ́n ṣe ń sálọ.

Ka pipe ipin Onídájọ́ 7

Wo Onídájọ́ 7:21 ni o tọ