Àwọn ọkùnrin Ísírẹ́lì ti búra ní Mísípà pé: “Kò sí ẹnìkan nínú wa tí yóò fi ọmọ obìnrin rẹ̀ fún ẹ̀yà Bẹ́ńjámínì ní ìyàwó.”