Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Nọ́ḿbà 31:3 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Mósè sì sọ fún àwọn ènìyàn pé, “Ẹ wọ ìhámọ́ra ogun fún àwọn kan nínú yín láti lọ da ojú ìjà kọ àwọn ọmọ Mídíánì láti gba ẹ̀san Olúwa lára wọn.

Ka pipe ipin Nọ́ḿbà 31

Wo Nọ́ḿbà 31:3 ni o tọ