Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Nọ́ḿbà 22:13 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Ní òwúrọ̀ ọjọ́ kejì Bálámù dìde ó sì sọ fún àwọn ìjòyè Bálákì pé, “Ẹ padà sí orílẹ̀ èdè yín, nítorí tí Olúwa ti kọ̀ láti jẹ́ kí n tẹ̀lé yín.”

Ka pipe ipin Nọ́ḿbà 22

Wo Nọ́ḿbà 22:13 ni o tọ