Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Nọ́ḿbà 20:21 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Nígbà tí Édómù sì kọ̀ jálẹ̀ láti jẹ́ kí wọn kọjá ní ilẹ̀ wọn, Ísírẹ́lì yípadà kúrò lọ́dọ̀ wọn.

Ka pipe ipin Nọ́ḿbà 20

Wo Nọ́ḿbà 20:21 ni o tọ