Nọ́ḿbà 16:38 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)
Èyí ni àwo tùràrí àwọn tí ó kú nítorí ẹ̀ṣẹ̀ wọn. Kí ẹ gún àwo tùràrí yìí, kí ẹ sì fi ṣe ìbòrí fún pẹpẹ, wọ́n jẹ́ mímọ́ nítorí pé wọ́n ti mú wọn wá ṣíwájú Olúwa. Kí wọ́n jẹ́ àmì fún àwọn ọmọ Ísírẹ́lì.”