12. Láti inú ẹ̀yà Dánì, Ámíélì ọmọ Gémálì;
13. Láti inú ẹ̀yá Áṣérì, Ṣétúrì ọmọ Míkáẹ́lì.
14. Láti inú ẹ̀yà Náfítanì, Nábì ọmọ Fófósì;
15. Láti inú ẹ̀yà Gádì, Géúlì ọmọ Mákì.
16. Wọ̀nyí ni orukọ àwọn ènìyàn tí Mósè rán láti lọ yẹ ilẹ̀ náà wò. (Ósísà ọmọ Núnì ni Mósè sọ ní Jóṣúà.)