Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Nehemáyà 11:26-34 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

26. Ní Jéṣúà, ní Móládà, ní Bétípélétì

27. Ní Háṣárì Ṣúálì, ní Bíáṣébà àti àwọn agbégbé rẹ̀.

28. Ní Ṣíkílágì, ní Mékónà àti àwọn ìletò rẹ̀,

29. ní Ẹni-rímónì, ní ṣórà, ní Járímútì,

30. Ṣánóà, Ádúlámù àti àwọn ìletò o wọn, ní Lákísì àti àwọn oko rẹ̀, àti ní Ásékà àti awọn ìletò rẹ̀. Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ń gbé láti Bíáṣébà títí dé àfonífojì Hínómì.

31. Àwọn ọmọ Bẹ́ńjámínì láti Gébì ń gbé ní Míkímásì, Áíjà, Bétélì àti àwọn ìletò rẹ̀.

32. Ní Ánátótì, Nóbù àti Ánáníyà,

33. Ní Háṣórì Rámà àti Gítaímù,

34. Ní Hádídì, Ṣébóimù àti Nébálátì,

Ka pipe ipin Nehemáyà 11