Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Nehemáyà 10:7-20 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

7. Mésúlámù, Ábíjà, Míjámínì,

8. Mááṣáyà, Bílígáì àti Ṣémáyà.Àwọn wọ̀nyí ni àwọn àlùfáà.

9. Àwọn ọmọ Léfì:Jéṣúà ọmọ Aṣanáyà, Bínúyì ọ̀kan nínú àwọn ọmọ Hénédédì, Kádímélì,

10. àti àwọn ẹlẹgbẹ́ ẹ wọn: Ṣébánáyà,Hódáyà, Kélítà, Péláyà, Hánánì,

11. Míkà, Réhébù, Hásábáyà,

12. Ṣákúrì, Ṣérébáyà, Ṣébánáyà,

13. Hódáyà, Bánì áti Benínù.

14. Àwọn olórí àwọn ènìyàn:Párósì, Páhátí-Móábù, Élámù, Ṣátù, Bánì,

15. Búnì, Áṣígádì, Bébáyì.

16. Àdóníjà, Bígífáyì, Ádínì,

17. Átérì, Heṣekáyà, Áṣúrì,

18. Hódáyà, Háṣámù, Béṣáyì,

19. Hárífì, Ánátótì, Nébáyì,

20. Mágípíásì, Mésúlámù, Héṣírì

Ka pipe ipin Nehemáyà 10