Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Jóòbù 30:26-30 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

26. Nígbà tí mo fojú sọ́nà fún àlàáfíà, ibi sì dé;nígbà tí mo dúró de ìmọ́lẹ̀, òkùnkùn sì dé.

27. Ikùn mí n ru kò sì sinmi; Ọjọ́ìpọ́njú ti dé bámi.

28. Èmí ń rìn kiri nínú ọ̀fọ̀, ṣùgbọ́nkì í ṣe nínú òòrùn; èmi dìdedúró ní àwùjọ mo sì kígbé fún ìrànlọ́wọ́.

29. Èmi ti di arákùnrin ìkòokò, èmidi ẹgbẹ́ àwọn ògòǹgò.

30. Àwọ̀ mi di dúdú ó sì ń bọ́wọ̀;egungun mi sì jórun fún oru.

Ka pipe ipin Jóòbù 30