Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Ísíkẹ́lì 26:19 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

“Èyí yìí ní Olúwa Ọlọ́run wí: Nígbà tí mo bá sọ ọ́ di ìlú ahoro, gẹ́gẹ́ bi àwọn ìlú tí a kò gbé inú wọn mọ́, àti nígbà tí èmi yóò mú ibú agbami òkun wá sí orí rẹ, omi ńlá yóò sì bò ọ́,

Ka pipe ipin Ísíkẹ́lì 26

Wo Ísíkẹ́lì 26:19 ni o tọ