Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Ísíkẹ́lì 22:31 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Nítorí náà ni mo ṣe ma da ìbínú mi sí wọn lórí; máa fí iná ìbínú mi run wọn: mo si ma fi ọ̀nà wọn gbẹ̀san lórí ara wọn, ní Olúwa Ọlọ́run wí.”

Ka pipe ipin Ísíkẹ́lì 22

Wo Ísíkẹ́lì 22:31 ni o tọ