Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Ísíkẹ́lì 11:17 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

“Nítorí náà, sọ pé: ‘Báyìí ni Olúwa Ọlọ́run wí: Èmi yóò kó wọn jọ kúrò láàrin àwọn orílẹ̀ èdè tí mo fọ́n wọn ká sí, Èmi yóò sì fún wọn ní ilẹ̀ Ísírẹ́lì padà.’

Ka pipe ipin Ísíkẹ́lì 11

Wo Ísíkẹ́lì 11:17 ni o tọ