Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Ékísódù 30:20 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Nígbàkígbà tí wọ́n bá wọ inú àgọ́ àjọ, wọ́n yóò wẹ̀ pẹ̀lú omi nítorí kí wọ́n má ba à kú. Bákan náà, nígbà tí wọ́n bá sún mọ́ ibi pẹpẹ láti ṣe ìṣìn, láti mú ẹbọ ti a fi iná sun wá fún Olúwa,

Ka pipe ipin Ékísódù 30

Wo Ékísódù 30:20 ni o tọ