Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Ékísódù 1:1-6 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

1. Ìwọ̀nyí ni àwọn orúkọ ọmọ Ísírẹ́lì tí wọ́n bá Jákọ́bù lọ sí Éjíbítì, ẹnìkọ̀ọ̀kan pẹ̀lú ìdílé rẹ̀:

2. Rúbẹ́nì, Símónì, Léfì àti Júdà,

3. Ísákárì, Ṣébúlúnì àti Bẹ́ńjámínì,

4. Dánì àti Náfítalì, Gádì àti Ásérì.

5. Àwọn ìran Jákọ́bù sì jẹ́ àádọ́rin ní àpapọ̀; Jóṣẹ́fù sì ti wà ní Éjíbítì.

6. Wáyìí o, Jóṣẹ́fù àti gbogbo àwọn arákùnrin rẹ̀ àti gbogbo ìran náà kú,

Ka pipe ipin Ékísódù 1