Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Dáníẹ́lì 2:47 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Ọba wí fún Dáníẹ́lì pé, “Dájúdájú Ọlọ́run rẹ ni Ọlọ́run àwọn ọlọ́run àti Olúwa àwọn ọba gbogbo àti olùfihàn àwọn àsírí, nítorí tí ìwọ lè fi àsírí yìí hàn.”

Ka pipe ipin Dáníẹ́lì 2

Wo Dáníẹ́lì 2:47 ni o tọ