10. Jéúṣì Ṣákíà àti Mírímà. Wọ̀nyí ni àwọn ọmọkùnrin Rẹ̀, olórí àwọn ìdílé.
11. Nípaṣẹ̀ Húṣímù ó ní Ábítúbù àti Élípálì.
12. Àwọn ọmọ Élípálì:Ébérì, Míṣámì, Ṣémédù (ẹni tí ó kọ́ Ónò àti Lódì pẹ̀lú àwọn ìletò àyíká Rẹ̀.)
13. Pẹ̀lú Béríà àti Ṣémà, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé ti àwọn tí ó ń gbé ní Áíjálónì àti àwọn tí ó lé àwọn olùgbé Gátì kúrò.
14. Áhíò, Ṣásákì Jérémílò,
15. Ṣébádíà, Árádì, Édérì
16. Míkáélì Íṣífà àti Jóhà jẹ́ àwọn ọmọ Béríà.
17. Ṣébàdíáhì, Mésúlámù Hésékì, Hébérì
18. Íṣíméráì, Íṣílíáhì àti Jóbábì jẹ́ àwọn ọmọ Élípálì.
19. Jákímì, Ṣíkírì, Ṣábídì,
20. Élíénáì Ṣílétaì Élíélì,
21. Ádáyà, Béráíáhì àti Ṣímírátì jẹ́ àwọn ọmọ, Ṣíméhì.