Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

1 Kíróníkà 3:9-24 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

9. Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Dáfídì yàtọ̀ sí àwọn ọmọ tí àlè bí fún un. Támárì sì ni arábìnrin wọn.

10. Ọmọ Sólómónì ni Réhóbóhámù,Ábíjà ọmọ Rẹ̀,Ásà ọmọ Rẹ̀,Jéhósáfátì ọmọ Rẹ̀,

11. Jéhórámù ọmọ Rẹ̀,Áhásáyà ọmọ Rẹ̀,Jóásì ọmọ Rẹ̀,

12. Ámásáyà ọmọ Rẹ̀,Ásáríyà ọmọ Rẹ̀,Jótamù ọmọ Rẹ̀,

13. Áhásì ọmọ Rẹ̀,Hesekíáyà ọmọ Rẹ̀,Mánásè ọmọ Rẹ̀,

14. Ámónì ọmọ Rẹ̀,Jósíà ọmọ Rẹ̀.

15. Àwọn ọmọ Jósíà:Àkọ́bí ọmọ Rẹ̀ ni Jóhánánì,èkejì ọmọ Rẹ̀ ni Jéhóíákímù,ẹ̀kẹta ọmọ Rẹ̀ ni Ṣédékíà,ẹ̀kẹ́rin ọmọ Rẹ̀ ni Ṣálúmù.

16. Àwọn ìran ọmọ Jéhóíákímù:Jékóníà ọmọ Rẹ̀,àti Ṣedékíà.

17. Àwọn ọmọ Jéhóíákímù tí a mú ní ìgbékùn:Ṣálátíélì ọmọ Rẹ̀ ọkùnrin,

18. Málíkírámù, Pédáíyà, Ṣénásárì, Jékámíà, Hósámà àti Nédábíà.

19. Àwọn ọmọ Pédáíyà:Ṣérúbábélì àti Ṣíméhì.Àwọn ọmọ Ṣérúbábélì:Mésúlámù àti Hánáníyà,Ṣélómítì ni arábìnrin wọn.

20. Àwọn márùnún mìíràn sì tún wà:Hásúbà, Óhéhì, Bérékíà, Hasádíà àti Jusabi-Hésédì.

21. Àwọn ọmọ Hánáníyà:Pélátíà àti Jeṣáíà, àti àwọn ọmọ Réfáíà, ti Árínánì, ti Ọbadíà àti ti ṣékáníà.

22. Àwọn ọmọ Ṣékáníà:Ṣémáíà àti àwọn ọmọ Rẹ̀:Hátúsì, Ígéálì, Báríà, Néáríà àti Ṣáfátì, mẹ́fà ni gbogbo wọn.

23. Àwọn ọmọ Néáríà:Élíóéníà; Hísíkíà àti Ásírí kámù, mẹ́ta ni gbogbo wọn.

24. Àwọn ọmọ Élíóéníà:Hódáíà, Élíásíbù, Pétéláéà, Ákúbù, Jóhánánì, Déláyà àti Ánánì, méje sì ni gbogbo wọn.

Ka pipe ipin 1 Kíróníkà 3