23. Ọlọ́run sì fi ìwà àìléwu fún un,àti nínú èyí ní a ó sì tì i lẹ́yìn, ojúrẹ̀ sì wà ní ipa ọ̀nà wọn.
24. A gbé wọn lékè nígbà díẹ̀; wọ́nkọjá lọ, a sì rẹ̀ wọ́n sílẹ̀; A sìmú wọn kúrò ní ọ̀nà, bí àwọnẹlòmìíràn, a sì ké wọn kúrò bí orí sírì itú ọkà bàbà.
25. “Ǹjẹ́, bí kò bá rí bẹ́ẹ̀ nísinsìn yìí,ta ni yóò mú mi ní èké,tí yóò sì sọ ọ̀rọ̀ mi di aláìníláárí?”