1. Éfúráímù ń jẹ afẹ́fẹ́;Ó n lépa afẹ́fẹ́ ìwọ̀ oòrùn ní gbogbo ọjọ́.Ó sì ń gbèrú nínú irọ́Ó dá májẹ̀mú pẹ̀lú ÁsíríàÓ si fi òróró ólífì ránsẹ́ sí Éjíbítì.
2. Olúwa ní ẹ̀sùn tí yóò fí kan Júdàyóò fìyà jẹ Jákọ́bù gẹ́gẹ́ bí ọ̀nà rẹ̀yóò sì sán fún-un gẹ́gẹ́ bí i ìṣe rẹ̀.