15. Áhímásì ní Náfítalì; ó fẹ́ Básémátì ọmọbìnrin Sólómónì ní aya;
16. Báánà ọmọ Húṣáì ní Ásérì àti ní Álótì;
17. Jèhósáfátì ọmọ Párúhà ni ó wà ní Ísákárì;
18. Síméì ọmọ Élà ni Bẹ́ńjámínì;
19. Gébérì ọmọ Úrì ní Gílíádì; orílẹ̀ èdè Ṣíhónì ọba àwọn ará Ámórì àti orílẹ̀ èdè Ógù ọba Básánì. Òun nìkan ni ìjòyè lórí ilẹ̀ náà.